Publicidade

Salmos 132

Orin fún ìgòkè.

1 Olúwa, rántí Dafidi

nínú gbogbo ìpọ́njú rẹ̀.

2 Ẹni ó ti búra fún Olúwa,

ó ṣe ìlérí fún alágbára Jakọbu .

3 Nítòótọ́, èmi yóò wọ inú àgọ́ ilé mi lọ,

bẹ́̀ èmi yóò gun orí àkéte mi.

4 Èmi yóò fi oorun fún ojú mi,

tàbí òògbé fún ìpéǹpéjú mi,

5 títí èmi ó fi ibi fún Olúwa,

ibùjókòó fún alágbára Jakọbu.

6 Kíyèsi i, àwa gbúròó rẹ̀ ni Efrata:

àwa i nínú oko ẹgàn náà.

7 Àwa ó lọ sínú àgọ́ rẹ̀:

àwa ó máa sìn níbi àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀

8 Olúwa, dìde ibi ìsinmi rẹ:

ìwọ, àti àpótí agbára rẹ.

9 a fi òdodo wọ àwọn àlùfáà rẹ:

àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ ó máa fún ayọ̀.

10 Nítorí Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀,

ṣe ojú ẹni òróró rẹ padà.

11 Olúwa ti búra nítòótọ́ fún Dafidi,

Òun yóò yípadà kúrò nínú rẹ̀,

nínú irú-ọmọ inú rẹ ni èmi ó gbé kalẹ̀ orí ìtẹ́ rẹ.

12 àwọn ọmọ rẹ̀ yóò pa májẹ̀mi mọ́

àti ̀mi èmi yóò kọ́ wọn,

àwọn ọmọ wọn pẹ̀yóò jókòó lórí ìtẹ́ rẹ láéláé.

13 Nítorí Olúwa ti yan Sioni:

ó ti fẹ́ fún ibùjókòó rẹ̀.

14 Èyí ni ibi ìsinmi mi láéláé:

níhìn-ín ni èmi yóò máa gbé:

nítorí mo fẹ́ .

15 Èmi yóò bùkún oúnjẹ rẹ̀ púpọ̀púpọ̀:

èmi yóò fi oúnjẹ tẹ́ àwọn tálákà rẹ̀ lọ́rùn.

16 Èmi yóò fi ìgbàlà wọ àwọn àlùfáà rẹ̀:

àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ yóò máa fún ayọ̀.

17 Níbẹ̀ ni èmi yóò gbé ìwo Dafidi yọ̀,

èmi ti ṣe ìlànà fìtílà kan fún ẹni òróró mi.

18 Àwọn ̀rẹ̀ ni èmi yóò fi ìtìjú wọ̀:

ṣùgbọ́n lára òun tìkára rẹ̀ ni adé yóò máa gbilẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-