Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 142

Maskili ti Dafidi. Nígbà ó nínú ihò òkúta. Àdúrà.

1 Èmi kígbe sókè Olúwa;

èmi gbé ohùn mi sókè Olúwa fún àánú.

2 Èmi àròyé sílẹ̀ níwájú rẹ̀,

bẹ́̀ èmi fi iṣẹ́ mi hàn níwájú rẹ̀.

3 Nígbà ̀mi ṣàárẹ̀ nínú mi,

ìwọ ni ẹni ó mọ ̀mi.

ipa ̀èmi ń rìn

ènìyàn ti dẹ okùn fún mi ìkọ̀kọ̀.

4 Wo ọwọ́ ̀tún mi ó i

ẹni ó ṣe àníyàn mi

èmi ààbò;

ẹni ó náání ọkàn mi.

5 Èmi kígbe , Olúwa:

èmi , "Ìwọ ni ààbò mi,

ìpín mi ilẹ̀ alààyè."

6 Fi etí igbe mi,

nítorí èmi nínú àìnírètí

gbà lọ́wọ́ àwọn ń lépa mi,

nítorí wọ́n lágbára lọ.

7 ọkàn mi jáde kúrò nínú túbú,

èmi máa yin orúkọ rẹ.

Nígbà náà ni àwọn olódodo yóò mi káàkiri

nítorí ìwọ yóò fi ̀pọ̀lọpọ̀ wọn ba mi ṣe.

Veja também