Publicidade

Salmos 144

Ti Dafidi.

1 Ìyìn Olúwa àpáta mi,

ẹni ó kọ́ ọwọ́ mi fún ogun,

àti ìka mi fún ìjà.

2 Òun ni Ọlọ́run ìfẹ́ mi àti odi alágbára mi,

ibi gíga mi àti olùgbàlà mi, asà mi,

ẹni èmi gbẹ́kẹ̀,

ẹni ó tẹrí àwọn ènìyàn ba lábẹ́ mi.

3 Olúwa, ni ènìyàn ìwọ fi ń ṣàníyàn fún un,

tàbí ọmọ ènìyàn ìwọ fi ń ronú nípa rẹ̀?

4 Ènìyàn èmi;

ọjọ́ rẹ̀ òjìji ń kọjá lọ.

5 Tẹ ̀run rẹ ba, Olúwa, o sọ̀kalẹ̀;

tọ́ àwọn òkè ńlá wọn yóò èéfín.

6 Rán mọ̀nàmọ́ó fọ́n àwọn ̀;

ta ọfà rẹ ó wọ́n .

7 Na ọwọ́ rẹ sílẹ̀ láti ibi gíga;

gbà o yọ nínú ewu

kúrò nínú omi ńlá:

kúrò lọ́wọ́ àwọn ọmọ àjèjì.

8 Ẹnu ẹni ó kún fún èké

ẹni ọwọ́ ̀tún rẹ̀ jẹ́ ìrẹ́jẹ.

9 Èmi yóò kọ orin tuntun

Ọlọ́run; lára ohun èlò orin

olókùn mẹ́wàá èmi yóò

kọ orin .

10 Òun ni ó fi ìgbàlà fún àwọn ọba,

ẹni ó gba Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ idà ìpanilára.

Lọ́wọ́ pípanirun. 11 Gbà o yọ nínú ewu

kúrò lọ́wọ́ àwọn ọmọ àjèjì

ẹnu wọn kún fún èké,

ọwọ́ ̀tún wọn jẹ́ ọwọ́ ̀tún èké.

12 àwọn ọmọkùnrin wa

ó dàbí igi gbígbìn ó dàgbà ni ìgbà èwe wọn,

àti ọmọbìnrin wa yóò dàbí òpó ilé

a ṣe ̀àfarawé ààfin.

13 Àká wa yóò kún

pẹ̀gbogbo onírúurú oúnjẹ

àgùntàn wa yóò pọ̀ si ẹgbẹ̀rún,

ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá oko wa:

14 àwọn màlúù wa yóò ru ẹrù wúwo

ó ìkọlù,

ó ìkólọ ìgbèkùn,

ó i igbe ìpọ́njú ìgboro wa.

15 Ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn náà ó irú ipò bẹ́̀,

ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn náà,

ẹni Ọlọ́run Olúwa ń ṣe.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-