Publicidade

Salmos 145

Saamu ìyìn. Ti Dafidi.

1 Èmi yóò gbé ga, Ọlọ́run ọba mi;

èmi yóò yin orúkọ rẹ̀ láé àti láéláé.

2 ojoojúmọ́ èmi yóò yìn ́

èmi yóò pòkìkí orúkọ rẹ láé àti láéláé.

3 Títóbi ni Olúwa. Òun ni ó yẹ láti fi ìyìn fún púpọ̀púpọ̀:

ẹni ó wọn títóbi rẹ̀.

4 Ìran kan yóò máa yin iṣẹ́ rẹ ìran mìíràn;

wọn yóò máa sọ iṣẹ́ agbára rẹ.

5 Wọn yóò máa sọ ìyìn ọláńlá rẹ ó lógo,

èmi yóò máa ṣe àṣàrò nínú iṣẹ́ ìyanu rẹ.

6 Wọn yóò sọ iṣẹ́ agbára rẹ ó ̀

èmi yóò kéde iṣẹ́ ńlá rẹ̀.

7 Wọn yóò ṣe ìrántí ̀pọ̀lọpọ̀

ìwà rere rẹ àti orin ayọ̀ òdodo rẹ.

8 Olóore-ọ̀fẹ́ ni Olúwa àti aláàánú

ó lọ́ra láti bínú ó ìfẹ́ púpọ̀.

9 Olúwa dára ẹni gbogbo;

ó àánú lórí ohun gbogbo ó .

10 Gbogbo ohun ìwọ ti ni

yóò máa yìn ́ Olúwa;

àwọn ẹni mímọ́ yóò máa pòkìkí rẹ.

11 Wọn yóò sọ ògo ìjọba rẹ

wọn yóò sọ̀rọ̀ agbára rẹ,

12 gbogbo ènìyàn le mọ iṣẹ́ agbára rẹ̀

àti ọláńlá ìjọba rẹ ó lógo.

13 Ìjọba rẹ ìjọba ayérayé ni,

àti ìjọba rẹ gbogbo ìrandíran.

14 Olúwa gbogbo àwọn ó ṣubú

ó gbé gbogbo àwọn ó tẹríba dìde.

15 Ojú gbogbo ènìyàn ń ́,

ó fún wọn oúnjẹ wọn àkókò ó yẹ.

16 Ìwọ ṣí ọwọ́ rẹ

ìwọ tẹ́ ìfẹ́ gbogbo ohun alààyè lọ́rùn.

17 Olúwa jẹ́ olódodo gbogbo ̀rẹ̀

àti ìfẹ́ rẹ̀ gbogbo ohun o .

18 Olúwa tòsí gbogbo àwọn ń é,

gbogbo ẹni ń é òtítọ́.

19 Ó ìfẹ́ àwọn ó bẹ̀rẹ̀ ṣẹ;

ó gbọ́ igbe wọn, ó gbà wọ́n.

20 Olúwa gbogbo àwọn ó ìfẹ́ sẹ

ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ẹni

búburú yóò parun.

21 Ẹnu mi yóò sọ̀rọ̀ ìyìn Olúwa.

Jẹ́ gbogbo ̀yín orúkọ rẹ̀ mímọ́ láé àti láéláé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-