Publicidade

Salmos 15

Saamu ti Dafidi.

1 Olúwa, ta ni yóò máa ṣe àtìpó nínú àgọ́ rẹ?

Ta ni yóò máa gbé òkè mímọ́ rẹ?

2 Ẹni ń rìn déédé

ó ń sọ òtítọ́,

láti inú ọkàn rẹ̀;

3 fi ahọ́n rẹ̀ sọ̀rọ̀ ẹni lẹ́yìn,

ṣe ibi aládùúgbò rẹ̀

sọ̀rọ̀ ̀gàn ẹnìkejì rẹ̀,

4 ojú ẹni ènìyànkénìyàn di gígàn

ṣùgbọ́n ó bọ̀wọ̀ fún àwọn ó bẹ̀Olúwa,

ẹni ó búra ibi ara rẹ̀

àní yípadà,

5 ó ń ni lówó láìsí èlé

gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ lòdì aláìlẹ́ṣẹ̀.

Ẹnikẹ́ni ó ṣe èyí

ni a yóò láéláé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-