Publicidade

Salmos 17

Àdúrà ti Dafidi.

1 Gbọ́, Olúwa, ̀bẹ̀ òtítọ́ mi;

fi etí igbe mi.

Tẹ́àdúrà mi

ti ètè ̀tàn jáde.

2 ìdáláre mi láti ̀dọ̀ rẹ;

ojú rẹ ó ohun ó tọ́.

3 Ìwọ ti dán àyà mi ,

ìwọ bẹ̀ òru, o ti wádìí mi,

ìwọ yóò ohunkóhun èmi ti pinnu ,

ẹnu mi yóò ṣẹ̀.

4 ó ṣe ti iṣẹ́ ènìyàn nípa ̀rọ̀ ẹnu rẹ,

èmi ti pa ara mi mọ́

kúrò ̀àwọn ìkà.

5 Ìrìn ti jẹ mọ́ ̀rẹ;

ẹsẹ̀ mi yóò yọ̀.

6 Èmi ́, Ọlọ́run, nítorí ìwọ yóò mi lóhùn

dẹ etí rẹ mi o gbọ́ àdúrà mi.

7 Fi ìṣeun ìyanu ìfẹ́ ńlá rẹ hàn

ìwọ ó fi ọwọ́ ̀tún rẹ gba àwọn ó gbẹ́kẹ̀

lọ́wọ́ àwọn ̀ó dìde wọn.

8 Pa mọ́ ẹyin ojú rẹ;

fi pamọ́ abẹ́ òjìji ìyẹ́ apá rẹ,

9 lọ́wọ́ àwọn ènìyàn búburú ń fóròó mi,

kúrò ọwọ́ àwọn ̀apani ó mi .

10 Wọ́n pa ọkàn aláìláàánú wọn mọ́,

wọ́n fi ẹnu wọn sọ̀rọ̀ ìgbéraga.

11 Wọ́n mi mọ́lẹ̀, wọ́n mi ,

pẹ̀ojú ìṣọ́ra láti ṣọ́ mi sílẹ̀.

12 Wọn dàbí i kìnnìún ebi ń pa fún ìjẹ,

àní kìnnìún ńlá ó ń ba níbi ìkọ̀kọ̀.

13 Dìde, Olúwa, dojúkọ wọ́n, rẹ̀ wọ́n sílẹ̀;

gbà sílẹ̀ lọ́wọ́ ẹni búburú nípa idà rẹ.

14 Olúwa, nípa ọwọ́ rẹ, gbà kúrò lọ́wọ́ irú àwọn ènìyàn bẹ́̀,

kúrò lọ́wọ́ àwọn ènìyàn ayé yìí, èrè wọn nínú ayé yìí.

Ìwọ ń pa ebi àwọn ìwọ fẹ́ràn lẹ́nu mọ́;

àwọn ọmọ wọn ̀pọ̀lọpọ̀,

wọ́n ọrọ̀ jọ fún àwọn ọmọ wọn.

15 Ṣùgbọ́n tèmi, èmi yóò máa wo ojú rẹ òdodo;

nígbà èmi , èmi yóò ìtẹ́lọ́rùn nígbà èmi àwòrán rẹ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-