Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 19

1 Àwọn ̀run ń sọ nípa ti ògo Ọlọ́run;

àwọsánmọ̀ ń sọ nípa ti iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.

2 Wọ́n ń fọhùn ọjọ́ ọjọ́;

wọ́n ń fi ìmọ̀ hàn alẹ́ alẹ́.

3 ohùn tàbí èdè

níbi a gbé gbọ́ ìró wọn.

4 19.4: Ro 10.18. Ohùn wọn jáde lọ gbogbo orílẹ̀ ayé,

̀rọ̀ wọn títí òpin ilẹ̀ ayé.

Ó ti kọ́ àgọ́ fún oòrùn nínú àwọn ̀run.

5 ó dàbí ọkọ ìyàwó ó ń jáde ti yàrá rẹ̀ ,

òun yọ alágbára ọkùnrin ó ń sáré ìje.

6 Ìjáde lọ rẹ̀ ni láti òpin ̀run

àti àyíká rẹ̀ ìpínlẹ̀ rẹ̀;

ohun ó pamọ́ kúrò nínú oore rẹ̀.

7 Pípé ni òfin Olúwa,

ó ń ọkàn padà.

̀Olúwa dánilójú,

ó sọ òpè di ọlọ́gbọ́n.

8 Ìlànà Olúwa tọ̀,

ó ń fi ayọ̀ fún ọkàn.

Àṣẹ Olúwa ni mímọ́,

ó ń fi ìmọ́lẹ̀ fún ojú.

Veja também