Publicidade

Salmos 19

Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi.

1 Àwọn ̀run ń sọ nípa ti ògo Ọlọ́run;

àwọsánmọ̀ ń sọ nípa ti iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.

2 Wọ́n ń fọhùn ọjọ́ ọjọ́;

wọ́n ń fi ìmọ̀ hàn alẹ́ alẹ́.

3 ohùn tàbí èdè

níbi a gbé gbọ́ ìró wọn.

4 Ohùn wọn jáde lọ gbogbo orílẹ̀ ayé,

̀rọ̀ wọn títí òpin ilẹ̀ ayé.

Ó ti kọ́ àgọ́ fún oòrùn nínú àwọn ̀run.

5 ó dàbí ọkọ ìyàwó ó ń jáde ti yàrá rẹ̀ ,

òun yọ alágbára ọkùnrin ó ń sáré ìje.

6 Ìjáde lọ rẹ̀ ni láti òpin ̀run

àti àyíká rẹ̀ ìpínlẹ̀ rẹ̀;

ohun ó pamọ́ kúrò nínú oore rẹ̀.

7 Pípé ni òfin Olúwa,

ó ń ọkàn padà.

̀Olúwa dánilójú,

ó sọ òpè di ọlọ́gbọ́n.

8 Ìlànà Olúwa tọ̀,

ó ń fi ayọ̀ fún ọkàn.

Àṣẹ Olúwa ni mímọ́,

ó ń fi ìmọ́lẹ̀ fún ojú.

9 Ìbẹ̀Olúwa mọ́,

ó ń faradà títí láéláé.

Ìdájọ́ Olúwa dájú

òdodo ni gbogbo wọn.

10 Wọn ṣọ̀wọ́n ju wúrà lọ,

ju wúrà o dára jùlọ,

wọ́n dùn ju oyin lọ,

àti ju afárá oyin lọ.

11 Nípa wọn ni a ti ṣí ìránṣẹ́ rẹ̀ létí;

nípa pípa wọ́n mọ́, èrè púpọ̀ ń bẹ.

12 Ta ni ó mọ àṣìṣe rẹ̀?

Dáríjì nínú àṣìṣe mi ó pamọ́.

13 Wẹ ìránṣẹ́ rẹ mọ́ kúrò nínú ̀ṣẹ̀ àmọ̀́n-mọ̀-;

ṣe jẹ wọn ó jẹ ọba lórí mi.

Nígbà náà èmi yóò dúró ṣinṣin,

èmi yóò ṣe aláìlẹ́bi kúrò nínú ̀ṣẹ̀ ńlá.

14 Jẹ́ ̀rọ̀ ẹnu mi àti àṣàrò ọkàn mi

ó jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà ojú rẹ,

Ìwọ Olúwa àpáta mi, àti Olùdáǹdè mi.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-