Publicidade

Salmos 22

Fún adarí orin. ohùn orin "àgbọ̀nrín òwúrọ̀." Saamu ti Dafidi.

1 Ọlọ́run mi, Ọlọ́run mi, èéṣe ìwọ fi kọ̀ sílẹ̀?

Èéṣe o fi jìnnà láti gbà ,

àní igbe ìkérora mi?

2 Ọlọ́run mi, ̀sán gangan ni mo kígbe, ṣùgbọ́n ìwọ mi ohùn:

àti òru èmi dákẹ́.

3 Ṣùgbọ́n síbẹ̀ ẹni mímọ́ ni Ìwọ;

ẹni ó tẹ ìyìn Israẹli .

4 Àwọn baba ńlá wa ìgbẹ́kẹ̀nínú rẹ;

wọ́n ìgbẹ́kẹ̀, ìwọ gbà wọ́n.

5 Ìwọ ni wọ́n sun ẹkún , wọ́n ìgbàlà;

ìwọ ni wọ́n gbẹ́kẹ̀, a dójútì wọ́n.

6 Ṣùgbọ́n kòkòrò mo jẹ́, í í ṣe ènìyàn;

mo di ẹlẹ́gàn àwọn ènìyàn, ẹlẹ́àwọn ènìyàn.

7 Gbogbo àwọn ó fi ṣe ẹlẹ́;

wọ́n yọ ètè ̀gàn wọn mi, wọ́n ń mi orí wọn .

8 "Ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ Olúwa;

jẹ́ Olúwa gbà á .

Jẹ́ ó gbà á ,

nítorí , ó ayọ̀ nínú rẹ̀."

9 Síbẹ̀ ìwọ ni ó ti mi láti inú;

ìwọ ni ó mi láìléwu, nígbà mo rọ̀ mọ́ ọmú ìyá mi.

10 Ìwọ ni a fi lọ́wọ́ láti inú ìyá mi ,

nígbà ìyá ti mi, ìwọ ni Ọlọ́run mi.

11 ṣe jìnnà mi,

nítorí ìyọnu súnmọ́ tòsí

ṣí ẹnìkan yóò ṣe ìrànlọ́wọ́.

12 ̀pọ̀ akọ màlúù mi ;

àwọn màlúù alágbára Baṣani rọ̀gbà mi .

13 Wọ́n ya ẹnu wọn mi i kìnnìún ń dọdẹ kiri,

ń ramúramù.

14 A jáde gẹ́gẹ́ omi,

gbogbo egungun mi ti yẹ̀ kúrò oríkèé rẹ̀.

Ọkàn mi dàbí i ìda;

ó yọ́ láàrín inú mi.

15 Agbára ti gbẹ àpáàdì,

ahọ́n tilẹ̀ mọ́ párí ̀rẹ̀kẹ́ mi;

ìwọ ti tẹ́ mi sínú eruku ikú.

16 Àwọn ajá mi ;

ìjọ àwọn ènìyàn ibi ti mi mọ́,

wọ́n gún mi lọ́wọ́, wọ́n gún mi lẹ́sẹ̀.

17 Mo ka gbogbo àwọn egungun mi;

àwọn tìkára wọn ń , wọ́n dójú mi.

18 Wọ́n pín aṣọ mi láàrín ara wọn

àní lórí aṣọ mi ni wọ́n ṣẹ́ gègé.

19 Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, ṣe jìnnà mi.

Háà! Olùrànlọ́wọ́ ̀ mi, yára fún àtìlẹ́yìn mi!

20 Gba ọkàn mi sílẹ̀ lọ́wọ́ idà,

àní ̀mi lọ́wọ́ agbára àwọn ajá.

21 Gba ọkàn mi sílẹ̀ lọ́wọ́ kìnnìún;

o gbà sílẹ̀ lọ́wọ́ ìwo àgbáǹréré.

22 Èmi yóò kéde orúkọ rẹ láàrín arákùnrin àti arábìnrin mi;

nínú ìjọ ni èmi yóò máa yìn ́.

23 ̀yin bẹ̀Olúwa, yìn ín!

Gbogbo ̀yin ìran Jakọbu, fi ògo fún un!

dìde fún un tẹ̀tẹ̀, ̀yin irú-ọmọ Israẹli!

24 Nítorí òun ṣátá, bẹ́̀ ni kórìíra

ìpọ́njú àwọn a ni lára;

fi ojú rẹ̀ pamọ́ fún mi

ṣùgbọ́n ó gbọ́ nígbà mo é.

25 Láti ̀dọ̀ rẹ̀ ni ìyìn mi yóò ti nínú àjọ ńlá;

̀jẹ́ rẹ̀ ni èmi yóò san níwájú àwọn o bẹ̀rẹ̀

26 tálákà yóò jẹ yóò ;

àwọn n Olúwa yóò yin

jẹ́ ̀rẹ̀ láààyè títí ayérayé!

27 Gbogbo òpin ayé ni yóò rántí

wọn yóò yípadà Olúwa,

àti gbogbo ìdílé orílẹ̀-èdè

ni wọn yóò jọ́sìn níwájú rẹ̀,

28 nítorí ìjọba ni ti Olúwa.

Òun ni ó ń pàṣẹ lórí àwọn orílẹ̀-èdè.

29 Bẹ́̀ náà ni gbogbo àwọn olówó ayé wọn yóò ṣe àsè, wọn yóò sìn;

gbogbo àwọn ó wọ inú ilẹ̀ lọ yóò kúnlẹ̀ iwájú rẹ̀

àti ẹni pa ọkàn ara rẹ̀ mọ́ ni ààyè.

30 Irú-ọmọ rẹ̀ yóò sìn ín;

a ó sọ fún àwọn ìran ń bọ̀ nípa Olúwa.

31 Wọn yóò polongo òdodo rẹ̀

àwọn ọmọ a ì ,

, òun ni ó ṣe èyí.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-