Publicidade

Salmos 25

Ti Dafidi.

1 Olúwa,

ìwọ ni mo gbé ọkàn mi sókè .

2 Ọlọ́run, èmi gbẹ́kẹ̀;

ṣe jẹ́ ojú ó

ṣe jẹ́ àwọn ̀mi ó yọ̀ .

3 Ẹni ó dúró ́

ojú yóò í,

àwọn ń ṣẹ̀ láìnídìí

ni ojú ó .

4 Fi ̀rẹ hàn , Olúwa,

kọ mi ipa tìrẹ;

5 ṣe amọ̀mi nínú òtítọ́ ̀ rẹ, o kọ́ mi,

nítorí ìwọ ni Ọlọ́run ìgbàlà mi;

ìwọ ni mo dúró gbogbo ọjọ́.

6 Rántí, Olúwa àánú àti ìfẹ́ ̀ rẹ̀ ńlá,

torí wọ́n ti ìgbà àtijọ́.

7 ṣe rántí àwọn ̀ṣẹ̀ ìgbà èwe mi

tàbí ìrékọjá mi;

gẹ́gẹ́ i ìfẹ́ rẹ̀ rántí mi

nítorí ìwọ dára, Ìwọ! Olúwa.

8 Rere àti ẹni ìdúró ṣinṣin Olúwa:

nítorí náà, ó kọ́ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ni ̀náà.

9 Ó ṣe amọ̀àwọn onírẹ̀lẹ̀ ni ohun ó dára,

ó kọ́ àwọn onírẹ̀lẹ̀ ̀rẹ̀.

10 Gbogbo ipa ̀Olúwa ni ìfẹ́ àti òdodo ó dúró ṣinṣin,

fún àwọn ó pa májẹ̀àti ̀rẹ̀ mọ́.

11 Nítorí orúkọ rẹ, Olúwa,

dárí ̀bi ̀ṣẹ̀ mi , nítorí ó tóbi.

12 Àwọn wo ni ó bẹ̀Olúwa?

Yóò kọ́ wọn ̀èyí wọn yóò yàn.

13 Wọn yóò lo ọjọ́ wọn nínú àlàáfíà,

àwọn ọmọ wọn yóò gba ilẹ̀ náà.

14 Olúwa fi ọkàn tán, àwọn o bẹ̀u rẹ̀;

ó sọ májẹ̀rẹ̀ di mọ̀ fún wọn.

15 Ojú mi gbé sókè sọ́dọ̀ Olúwa,

nítorí yóò yọ ẹsẹ̀ mi kúrò nínú àwọ̀n náà.

16 Yípadà mi, o ṣe oore fún mi;

nítorí mo nìkan , mo di olùpọ́njú.

17 lẹ́yìn kúrò nínú ìpọ́njú àyà mi;

o yọ kúrò nínú ìpọ́njú mi.

18 Kíyèsi ìjìyà àti wàhálà mi,

o dárí gbogbo ̀ṣẹ̀ mi .

19 Kíyèsi ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ̀mi,

wọn kórìíra mi pẹ̀ìwà ìkà wọn.

20 Pa ọkàn mi mọ́, o gbà sílẹ̀;

ṣe jẹ́ a fi sínú ìtìjú,

nítorí ìwọ ni ibi ìsádi mi.

21 Jẹ́ òtítọ́ inú àti ìdúró ṣinṣin ó pa mọ́;

nítorí mo dúró ́.

22 Ra Israẹli padà, Ìwọ Ọlọ́run,

nínú gbogbo ìṣòro rẹ̀!

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-