Publicidade

Salmos 33

1 yọ̀ nínú Olúwa, ̀yin olódodo;

ìyìn si yẹ fún ẹni dídúró ṣinṣin.

2 yin Olúwa pẹ̀dùùrù;

máa fi ohun èlò olókùn mẹ́wàá kọrin i.

3 kọ orin tuntun i;

máa fi ọgbọọgbọ́n lu ohun èlò orin i, pẹ̀ariwo.

4 Nítorí ̀rọ̀ Olúwa dúró ṣinṣin,

gbogbo iṣẹ́ rẹ̀ ni à ń ṣe nínú òtítọ́.

5 Ó fẹ́ òtítọ́ àti ìdájọ́;

ilé ayé kún fún ìdúró ṣinṣin àti àánú Olúwa.

6 Nípasẹ̀ ̀rọ̀ Olúwa ni a ṣe àwọn ̀run,

àti gbogbo àwọn ẹgbẹ́ ogun wọn nípa ìmísí ẹnu rẹ̀.

7 Ó àwọn omi òkun jọ gẹ́gẹ́ èyí ó nínú ìgò;

ó fi ibú ṣe ilé ìṣúra gbogbo.

8 Jẹ́ gbogbo ayé ó bẹ̀Olúwa:

jẹ́ gbogbo àwọn olùgbé ayé ó nínú ìbẹ̀rẹ̀.

9 Nítorí ó sọ̀rọ̀, ó ti bẹ́̀;

ó pàṣẹ ó dúró ṣinṣin.

10 Olúwa ti ìmọ̀ràn àwọn orílẹ̀-èdè asán;

ó àrékérekè àwọn ènìyàn di ṣíṣákì í.

11 Ìgbìmọ̀ Olúwa dúró títí ayérayé,

àní ìrò inú rẹ̀ láti ìrandíran ni.

12 Ìbùkún ni fún orílẹ̀-èdè náà, Ọlọ́run ẹni Olúwa jẹ́ tirẹ̀,

àti àwọn ènìyàn náà ó ti yàn ṣe ìní rẹ̀.

13 Olúwa láti ̀run ;

Ó gbogbo ìran ènìyàn.

14 Níbi ó ti jókòó lórí ìtẹ́

Ó wo gbogbo àwọn olùgbé ayé

15 ẹni ó ṣe àyà wọn bákan náà,

ó kíyèsi ìṣe wọn.

16 A gba ọba kan nípasẹ̀ ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọmọ-ogun;

jagunjagun a gbà sílẹ̀ nípa agbára ńlá rẹ̀.

17 Ohun asán ni ẹṣin fún ìṣẹ́gun;

bẹ́̀ ni yóò fi agbára ńlá rẹ̀ gbani sílẹ̀.

18 ó, ojú Olúwa lára àwọn ó bẹ̀rẹ̀,

àti lára àwọn ó ìrètí nínú ìfẹ́ rẹ̀ ó dúró ṣinṣin.

19 Láti gba ọkàn wọn kúrò lọ́wọ́ ikú

àti láti pa wọ́n mọ́ láààyè lọ́wọ́ ìyàn.

20 Ọkàn wa dúró de Olúwa;

òun ni ìrànlọ́wọ́ wa àti asà wa.

21 Ọkàn wa yọ̀ nínú rẹ̀,

nítorí , àwa gbẹ́kẹ̀orúkọ rẹ mímọ́.

22 àánú rẹ, Olúwa, ó lára wa,

àní gẹ́gẹ́ àwa ti ń ṣe ìrètí nínú rẹ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-