Publicidade

Salmos 4

Fún adarí orin. Pẹ̀ohun èlò orin olókùn. Saamu ti Dafidi.

1 mi lóhùn nígbà mo ́,

ìwọ Ọlọ́run òdodo mi.

Fún mi ìdáǹdè nínú ìpọ́njú mi;

ṣàánú fún mi, o gbọ́ àdúrà mi.

2 Báwo ni yóò ṣe pẹ́ , ̀yin ọmọ ènìyàn, ó ṣe sọ ògo mi di ìtìjú?

Báwo ni yóò ṣe pẹ́ , ̀yin yóò ṣe fẹ́ràn ìtànjẹ àti ̀yin yóò fi máa ọlọ́run èké?

3 Ṣùgbọ́n mọ̀ , Olúwa ti ya ẹni olódodo sọ́tọ̀ fún ara rẹ̀;

Olúwa yóò gbọ́ nígbà mo é.

4 bínú ṣe ṣẹ̀,

nígbà lórí ibùsùn yín,

ọkàn yín sọ̀rọ̀, ó dákẹ́ jẹ́.

5 ẹbọ òdodo

gbẹ́kẹ̀Olúwa.

6 ̀pọ̀lọpọ̀ ń béèrè , "Ta ni yóò ṣe rere fún wa?"

Olúwa, jẹ́ ojú rẹ mọ́lẹ̀ wa lára,

7 Ìwọ ti fi ayọ̀ púpọ̀ kún ọkàn mi

ju ìgbà hóró irúgbìn àti wáìnì tuntun wọ́n pọ̀ fún mi lọ.

8 Èmi yóò dùbúlẹ̀, èmi ó sùn àlàáfíà,

nítorí ìwọ nìkan, Olúwa,

ni o mi gbé láìléwu.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-