Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 42

Fún adarí orin. Maskili ti àwọn ọmọ Kora.

1 àgbọ̀nrín ti ń hẹlẹ ipa odò omi,

bẹ́̀ ni ọkàn mi ń hẹlẹ Ọlọ́run.

2 Òùngbẹ Ọlọ́run ń gbẹ ọkàn mi, fún Ọlọ́run alààyè.

Nígbà wo ni èmi ó lọ Ọlọ́run?

3 Oúnjẹ mi ni omijé mi

̀sán àti òru,

nígbà àwọn ènìyàn ń fún mi gbogbo ọjọ́ ,

"Ọlọ́run rẹ ?"

4 Nígbà mo rántí nǹkan yìí,

èmi ọkàn mi jáde nínú mi:

èmi ti ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn lọ,

èmi wọn lọ ilé Ọlọ́run

pẹ̀ohùn ayọ̀ àti ìyìn,

pẹ̀̀pọ̀ ènìyàn ń pa ọjọ́ mímọ́ mọ́.

5 Èéṣe o fi ń rẹ̀wẹ̀, ìwọ ọkàn mi?

Èéṣe ara rẹ fi lélẹ̀ nínú mi?

Ìwọ ṣe ìrètí ti Ọlọ́run,

nítorí èmi yóò à máa yìn ín,

Olùgbàlà mi àti Ọlọ́run mi.

6 Ọlọ́run mi, ọkàn mi ń rẹ̀wẹ̀nínú mi:

nítorí náà, èmi ó rántí rẹ

láti ilẹ̀ Jordani ,

láti Hermoni láti òkè Mibsari.

7 Ibú omi ń pe ibú omi

nípa híhó omi ṣíṣàn rẹ̀

gbogbo rírú omi àti bíbì omi rẹ̀

mọ́lẹ̀.

8 ̀sán Olúwa ran ìfẹ́ rẹ̀,

àti ni àṣálẹ́ ni orin rẹ̀ pẹ̀mi

àdúrà Ọlọ́run ayé mi.

9 Èmi fún Ọlọ́run àpáta mi,

"Èéṣe ìwọ fi gbàgbé mi?

Èéṣe èmi o fi máa rìn nínú ìbànújẹ́,

nítorí ìnilára ̀?"

10 ẹni idà egungun mi ni ̀gàn

àwọn ̀mi ń gàn ,

wọn ti ń béèrè gbogbo ọjọ́.

"Níbo ni Ọlọ́run rẹ ?"

11 Èéṣe ìwọ fi ń rẹ̀wẹ̀, ìwọ ọkàn mi?

Èéṣe ara rẹ fi lélẹ̀ nínú mi?

Fi ìrètí rẹ sínú Ọlọ́run,

nítorí èmi yóò máa yìn ín, Òun ni

Olùgbàlà mi àti Ọlọ́run mi.

Veja também