Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 46

Fún adarí orin. Ti àwọn ọmọ Kora. Gẹ́gẹ́ ti alamoti. Orin.

1 Ọlọ́run ni ààbò àti agbára wa

ó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ ìgbà ìpọ́njú.

2 Nítorí náà àwa yóò bẹ̀, a tilẹ̀ ṣí ayé ìdí,

òkè ṣubú sínú Òkun.

3 omi rẹ̀ tilẹ̀ ń ó ń

àwọn òkè ńlá tilẹ̀ ń pẹ̀ọwọ́ agbára rẹ̀. Sela.

4 Odò ńlá kan ṣíṣàn rẹ̀ inú ìlú Ọlọ́run dùn,

ibi mímọ́, níbi ti ̀gá-ògo ń gbé.

5 Ọlọ́run pẹ̀rẹ̀, yẹ̀:

Ọlọ́run yóò ràn án lọ́wọ́ kùtùkùtù òwúrọ̀.

6 Àwọn orílẹ̀-èdè ń bínú, àwọn ilẹ̀ ọba ṣubú,

ó gbé ohun rẹ̀ sókè, ayé yọ̀.

7 Olúwa àwọn ọmọ-ogun pẹ̀wa,

Ọlọ́run Jakọbu ni ààbò wa.

8 wo iṣẹ́ Olúwa

irú ahoro ó ṣe ayé.

9 O ̀tẹ̀ tán de òpin ilẹ̀ ayé

ó ṣẹ́ ọrun, ó ̀kọ̀ méjì

ó fi kẹ̀kẹ́ ogun jóná.

10 dúró jẹ́́, mọ̀ èmi Ọlọ́run.

A ó gbé mi ga nínú àwọn orílẹ̀-èdè,

a ó gbé mi ga ayé.

11 Olúwa àwọn ọmọ-ogun pẹ̀wa;

Ọlọ́run Jakọbu ni ààbò wa.

Veja também