Publicidade

Salmos 5

Fún adarí orin. Fún ohun èlò orin fífọn. Saamu ti Dafidi.

1 Fi etí ̀rọ̀ mi, Olúwa,

kíyèsi àròyé mi.

2 Fi etí sílẹ̀ igbe mi fún ìrànlọ́wọ́,

ọba mi àti Ọlọ́run mi,

nítorí ìwọ ni mo gba àdúrà .

3 òwúrọ̀, Olúwa, ìwọ yóò gbọ́ ohùn mi;

òwúrọ̀, èmi yóò gbé ̀bẹ̀ mi iwájú rẹ̀

èmi yóò dúró ìrètí.

4 Nítorí ìwọ í ṣe Ọlọ́run ó inú dídùn búburú;

bẹ́̀ ni ẹni ibi le è gbé.

5 Àwọn agbéraga le è dúró

níwájú rẹ̀.

Ìwọ kórìíra gbogbo àwọn aṣebi;

6 ìwọ yóò pa àwọn ń ṣe èké run.

Apani àti ẹni ̀tàn ènìyàn

ni Olúwa yóò kórìíra.

7 Ṣùgbọ́n èmi, nípa títóbi àánú rẹ̀,

èmi yóò sínú ilé rẹ̀;

tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀ ni èmi yóò tẹríba

ìhà tẹmpili mímọ́ rẹ̀.

8 Tọ́ mi, Olúwa, nínú òdodo rẹ,

nítorí àwọn ̀mi,

̀rẹ tọ́ níwájú mi.

9 ̀rọ̀ kan ẹnu wọn a gbàgbọ́;

ọkàn wọn kún fún ìparun.

̀̀fun wọn ni isà òkú ó ṣí sílẹ̀;

pẹ̀ahọ́n wọn ni wọ́n ń sọ ̀tàn.

10 wọn lẹ́bi Ọlọ́run!

Jẹ́ rìkíṣí wọn jẹ́ ìṣubú wọn.

wọn jáde nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ ̀ṣẹ̀ wọn,

nítorí wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ .

11 Ṣùgbọ́n, jẹ́ gbogbo àwọn ó sádi ́ ó yọ̀;

jẹ wọn máa kọrin fún ayọ̀ títí.

Tan ààbò rẹ sórí wọn,

àti àwọn ó fẹ́ràn orúkọ rẹ yóò máa yọ̀ nínú rẹ.

12 Dájúdájú, Olúwa, ìwọ bùkún olódodo;

ìwọ fi ojúrere rẹ wọn asà.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-