Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 51

2 Wẹ gbogbo àìṣedéédéé mi kúrò

o wẹ̀ mi mọ́ kúrò nínú ̀ṣẹ̀ mi!

3 Nítorí mo mọ̀ gbogbo ̀ṣẹ̀ mi,

nígbà gbogbo ni ̀ṣẹ̀ mi níwájú mi.

4 51.4: Ro 3.4. , ìwọ nìkan ṣoṣo, ni mo dẹ́ṣẹ̀

ni mo ṣe búburú níwájú rẹ̀,

a láre nígbà ìwọ ń sọ̀rọ̀,

o le láìlẹ́bi, nígbà ìwọ ń ṣe ìdájọ́.

Veja também