Publicidade

Salmos 59

Fún adarí orin. ohùn orin "ṣe parun." Ti Dafidi. Miktamu. Nígbà Saulu rán àwọn olùṣọ́ ilé Dafidi òun le i pa.

1 Gbà lọ́wọ́ àwọn ̀à mi, Ọlọ́run;

dáàbò kúrò lọ́dọ̀ àwọn ó dìde mi.

2 Gbà lọ́wọ́ àwọn oníṣẹ́ búburú

o gbà lọ́wọ́ àwọn ènìyàn ń pòǹgbẹ ̀jẹ̀.

3 ó, wọ́n ṣe ba bùba !

Àwọn alágbára ń gbìmọ̀ lòdì mi

í ṣe nítorí ìrékọjá mi tàbí ̀ṣẹ̀ , Olúwa.

4 Èmi ṣe àìṣedéédéé kan, síbẹ̀ wọ́n sáré wọ́n ṣetán láti kọlù .

Dìde fún ìrànlọ́wọ́ mi, o wo àìlera mi.

5 Olúwa Ọlọ́run Alágbára,

Ọlọ́run Israẹli,

dìde fún ara rẹ o àwọn orílẹ̀-èdè ;

ṣe ṣàánú fún àwọn olùrékọjá búburú . Sela.

6 Wọ́n padà àṣálẹ́,

wọ́n ń gbó àwọn ajá,

wọ́n ń rìn ìlú náà káàkiri.

7 Kíyèsi ohun wọ́n jáde ẹnu:

wọn ń idà jáde láti ètè wọn,

wọ́n , "Ta ni ó gbọ́ ̀rọ̀ wa?"

8 Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, yóò fi wọ́n rẹ́rìn-ín,

Ìwọ ó yọ ṣùtì gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè.

9 Ìwọ agbára mi, èmi ó máa kọrin ìyìn ;

nítorí ìwọ Ọlọ́run ni ààbò mi,

10 Ọlọ́run àánú mi ni yóò ṣáájú mi.

Ọlọ́run yóò jẹ́ èmi ìfẹ́ mi lára àwọn ̀mi.

Yóò jẹ́ n yọ ayọ̀ ìṣẹ́gun lórí ìfẹ́ àwọn ̀mi.

11 Ṣùgbọ́n ṣe pa wọ́n, Olúwa asà wa,

àwọn ènìyàn mi ba à gbàgbé.

Nínú agbára rẹ, jẹ́ wọn máa rìn kiri,

o rẹ̀ wọ́n sílẹ̀.

12 Nítorí ̀ṣẹ̀ ẹnu wọn,

̀rọ̀ ètè wọn,

a wọn nínú ìgbéraga wọn.

Nítorí èébú àti èké wọn ń sọ,

13 pa wọ́n run nínú ìbínú,

run wọ́n di ìgbà wọn mọ́.

Nígbà náà ni yóò di mọ̀ òpin ayé

Ọlọ́run jẹ ọba lórí Jakọbu. Sela.

14 Wọ́n padà àṣálẹ́,

wọn ń gbó àwọn ajá

wọ́n ń rin ìlú náà káàkiri.

15 Wọ́n ń rin kiri fún oúnjẹ

wọ́n ń yán nígbà wọn .

16 Ṣùgbọ́n èmi ó kọrin agbára rẹ,

n ó kọrin ìfẹ́ rẹ òwúrọ̀;

nítorí ìwọ ni ààbò mi,

ibi ìsádi mi ìgbà ìpọ́njú.

17 Ìwọ agbára mi, èmi ó kọrin ìyìn ;

ìwọ, Ọlọ́run, ààbò mi, Ọlọ́run ìfẹ́ mi.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-