Publicidade

Salmos 66

Fún adarí orin. Orin. Saamu.

1 ìhó ayọ̀ Ọlọ́run, ̀yin ilẹ̀ gbogbo!

2 kọrin ọlá orúkọ rẹ̀;

kọrin ìyìnsí i.

3 fún Ọlọ́run , "Ìwọ ti ̀nínú iṣẹ́ rẹ!

Nípa ̀pọ̀ agbára rẹ

ni àwọn ̀rẹ yóò fi sìn ́.

4 Gbogbo ayé ń wólẹ̀ fún ;

wọn ń kọrin ìyìn ,

wọ́n ń kọrin ìyìn orúkọ rẹ." Sela.

5 wo ohun Ọlọ́run ṣe,

iṣẹ́ rẹ̀ ti ̀àwọn ọmọ ènìyàn!

6 Ó òkun padà ilẹ̀ gbígbẹ,

wọ́n fi ẹsẹ̀ rin inú omi kọjá,

níbẹ̀ ni àwa yọ̀ nínú rẹ̀.

7 Ó ń jẹ ọba títí láé nípa agbára rẹ̀,

ojú rẹ̀ ń wo orílẹ̀-èdè

àwọn ọlọ̀tẹ̀ ṣe gbé ara wọn ga. Sela.

8 yin Ọlọ́run wa, ̀yin ènìyàn,

jẹ́ a ni gbọ́ ohùn ìyìn rẹ̀;

9 Ó ti ààbò bo ̀wa,

jẹ́ ẹsẹ̀ wa ó yẹ̀.

10 Nítorí ìwọ, Ọlọ́run, dán wa ;

ìwọ dán wa a ń dán fàdákà .

11 Ìwọ wa sínú ̀wọ̀n

o di ẹrù ̀yìn wa.

12 Ìwọ àwọn ènìyàn gún orí

àwa la iná àti omi kọjá

ṣùgbọ́n ìwọ wa ibi ̀pọ̀.

13 Èmi ó tẹmpili rẹ pẹ̀ọrẹ ẹbọ sísun,

n ̀jẹ́ mi ṣẹ ,

14 ̀jẹ́ ètè mi jẹ́, ẹnu mi sọ

nígbà mo nínú ìṣòro.

15 Èmi ó ẹbọ sísun ọlọ́ràá ,

àti ẹbọ ̀àgbò;

èmi ó akọ màlúù àti ewúrẹ́. Sela.

16 gbọ́ gbogbo ̀yin ó bẹ̀Ọlọ́run;

jẹ́ n sọ ohun ó ṣe fún mi.

17 Mo fi ẹnu mi kígbe sókè i,

ìyìn rẹ̀ ẹnu mi.

18 èmi gba ̀ṣẹ̀ àyà mi,

Olúwa yóò gbọ́ ohùn mi;

19 ṣùgbọ́n Ọlọ́run gbọ́ nítòótọ́

ó ti gbọ́ ohùn mi nínú àdúrà.

20 Ìyìn ni fún Ọlọ́run

ẹni kọ àdúrà mi

tàbí ìfẹ́ rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ mi!

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-