Publicidade

Salmos 79

Saamu ti Asafu.

1 Ọlọ́run, àwọn orílẹ̀-èdè ti ilẹ̀ ìní rẹ;

wọ́n ti ba tẹmpili mímọ́ rẹ jẹ́,

wọn di Jerusalẹmu òkìtì àlàpà.

2 Wọn ti fi ara òkú àwọn ìránṣẹ́ rẹ

fún àwọn ẹyẹ ojú ̀run oúnjẹ,

ẹran-ara àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ fún ẹranko ilẹ̀.

3 Wọ́n tu ̀jẹ̀ jáde gẹ́gẹ́ omi

Jerusalẹmu ,

ṣí àwọn yóò sìn wọ́n.

4 Àwa di ohun ̀gàn àwọn ó wa ,

àbùkù àti ìfiṣe ẹlẹ́àwọn ó wa .

5 Nígbà wo, Olúwa? ìwọ ó máa bínú títí láé?

Yóò ti pẹ́ ti owú rẹ yóò ha iná?

6 ìbínú rẹ jáde orílẹ̀-èdè

ìmọ̀ rẹ,

lórí àwọn ìjọba

pe orúkọ rẹ;

7 nítorí wọ́n ti run Jakọbu

wọ́n sọ ibùgbé rẹ di ahoro.

8 ṣe ka ̀ṣẹ̀ àwọn baba wa wa lọ́rùn

jẹ́ àánú rẹ kánkán láti wa,

nítorí a rẹ̀ sílẹ̀ gidigidi.

9 Ràn lọ́wọ́, Ọlọ́run Olùgbàlà wa,

fún ògo orúkọ rẹ;

gbà o dárí ̀ṣẹ̀ wa

nítorí orúkọ rẹ.

10 Àwọn orílẹ̀-èdè yóò máa ,

"Níbo ni Ọlọ́run wọn ?"

ojú wa, a mọ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè

ó gbẹ̀san àwọn ̀jẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ a jáde.

11 Jẹ́ ìmí ̀dùn oǹdè náà síwájú rẹ,

gẹ́gẹ́ títóbi agbára rẹ

ìwọ ṣe ìtọ́àwọn ti a lẹ́bi ikú.

12 San án padà àyà àwọn aládùúgbò wa nígbà méje

nípa ̀gàn wọn ti gàn ́ Olúwa.

13 Nígbà náà àwa ènìyàn rẹ,

àti àgùntàn pápá rẹ,

yóò fi ọpẹ́ fún títí láé;

láti ìran ìran

ni àwa ó fi ìyìn rẹ hàn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-