Publicidade

Salmos 81

Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ ti gittiti. Ti Asafu.

1 Kọrin sókè Ọlọ́run agbára wa

ìhó ayọ̀ Ọlọ́run Jakọbu!

2 orin mímọ́, ìlù ,

tẹ dùùrù dídùn pẹ̀ohun èlò orin mímọ́.

3 fún ìpè oṣù tuntun

àní nígbà a yàn;

ọjọ́ àjọ wa ó ìrònú.

4 Èyí ni àṣẹ fún Israẹli,

àti òfin Ọlọ́run Jakọbu.

5 Ó fi múlẹ̀ gẹ́gẹ́ ìlànà fún Josẹfu

nígbà ó la ilẹ̀ Ejibiti .

Níbi a ti gbọ́ èdè wa.

6 Ó , "Mo gbé àjàgà kúrò èjìká yín,

a ọwọ́ wọn sílẹ̀ kúrò nínú apẹ̀rẹ̀.

7 Nínú ìnilára ni mo gbà yín ,

mo a yín lóhùn nínú ìkọ̀kọ̀ àrá,

mo dán an yín odò Meriba. Sela.

8 "Gbọ́, ̀yin ènìyàn mi, èmi ó kìlọ̀ fún un yín,

ìwọ fetí mi, ìwọ Israẹli.

9 ̀yin yóò Ọlọ́run ilẹ̀ mìíràn láàrín yín;

̀yin yóò foríbalẹ̀ fún Ọlọ́run àjèjì.

10 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ,

ẹni ó un yín jáde láti Ejibiti.

la ẹnu yín gbòòrò, èmi yóò kún un.

11 "Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi yóò gbọ́ tèmi;

Israẹli tẹríba fún mi.

12 Nítorí náà ni mo ṣe fi wọ́n fún ọkàn líle wọn

láti máa rìn ̀̀tàn wọn.

13 "àwọn ènìyàn mi yóò gbọ́ tèmi

Israẹli yóò tẹ̀̀mi,

14 kánkán ni èmi yóò ṣẹ́gun àwọn ̀wọn

n ọwọ́ mi padà ̀wọn!

15 Àwọn ó kórìíra Olúwa yóò tẹríba níwájú rẹ̀.

Ìjìyà wọn yóò pẹ́ títí láé.

16 Ṣùgbọ́n a ó fi ọkà ó dára bọ́ yín

èmi ó tẹ́ yín lọ́rùn pẹ̀oyin inú àpáta."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-