Publicidade

Salmos 89

Maskili ti Etani ará Esra.

1 Èmi kọrin títóbi ìfẹ́ Olúwa títí láé;

pẹ̀ẹnu mi èmi yóò jẹ́ a mọ òtítọ́ rẹ láti ìran ìran.

2 Èmi ó , ìfẹ́ rẹ dúró títí láé,

ìwọ gbe òtítọ́ rẹ kalẹ̀ ̀run fúnra rẹ̀.

3 89.3-4: Sm 132.11; Ap 2.30. Ìwọ , "Èmi ti májẹ̀pẹ̀àwọn àyànfẹ́ mi

mo ti búra fún Dafidi ìránṣẹ́ mi.

4 Èmi ó fi ìdí irú-ọmọ rẹ múlẹ̀ títí láé

èmí ó máa gbe ìtẹ́ rẹ láti ìran ìran.’ "

5 Àwọn ̀run yóò máa yin iṣẹ́ ìyanu rẹ, Olúwa,

òtítọ́ rẹ ni ìpéjọpọ̀ àwọn ẹni mímọ́.

6 Ta ni ó ̀run a fiwé Olúwa?

Ta ni nínú àwọn ọmọ alágbára ti a fiwé Olúwa?

7 Nínú àjọ ìgbìmọ̀ ẹni mímọ́, wọ́n bẹ̀Ọlọ́run gidigidi;

ó ìbùyìn fún ju gbogbo àwọn ó i .

8 Olúwa Ọlọ́run alágbára, ta dàbí rẹ

ìwọ jẹ́ alágbára, Olúwa, òtítọ́ rẹ .

9 Ìwọ ń darí ríru omi Òkun;

nígbà ó ru àwọn omi sókè, ìwọ wọn parọ́rọ́.

10 Ìwọ ni ó ti ya Rahabu pẹ́rẹpẹ̀rẹ

ẹni a pa;

ìwọ ti fi apá ọwọ́ agbára rẹ

àwọn ̀rẹ .

11 Tìrẹ àwọn ̀run, ayé pẹ̀jẹ́ tìrẹ:

ayé àti ohun gbogbo ó nínú rẹ̀:

ìwọ ti gbé wọn kalẹ̀.

12 Gúúsù àti àríwá ìwọ ni ó wọn;

Tabori àti Hermoni ń fi ayọ̀ yin orúkọ rẹ.

13 Ìwọ apá agbára;

agbára ọwọ́ rẹ, gíga ọwọ́ ̀tún rẹ.

14 Òdodo àti òtítọ́ ni ìpìlẹ̀ ìtẹ́ rẹ:

ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ àti òtítọ́ ń lọ síwájú rẹ.

15 Ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn wọn mọ ohùn ayọ̀ ,

Olúwa wọ́n ó máa rìn ìmọ́lẹ̀ ojú rẹ.

16 Wọn ń ṣògo nínú orúkọ rẹ̀ gbogbo ọjọ́,

wọn ń yin òdodo rẹ.

17 Nítorí ìwọ ni ògo agbára wọn;

nípa ojúrere ni ìwo ń ṣògo.

18 Nítorí ti Olúwa ni asà wa,

ọba wa ni Ẹni Mímọ́ Israẹli.

19 Nígbà náà ni ìwọ sọ̀rọ̀ nínú ìran, àwọn olóòtítọ́ rẹ, ,

"Èmi ti gbé adé kalẹ̀ sórí ẹni ó lágbára,

èmi ti gbé ẹni a yàn láti ̀dọ̀ àwọn ènìyàn ga.

20 89.20: Ap 13.22. Èmi ti Dafidi ìránṣẹ́ mi;

pẹ̀òróró mímọ́ mi ni mo fi yàn án.

21 Ìgbà gbogbo ni ọwọ́ mi yóò máa pẹ̀rẹ̀

apá yóò fi agbára fún un.

22 Àwọn ̀yóò borí rẹ̀,

àwọn ènìyàn búburú yóò rẹ̀ ́ sílẹ̀.

23 Èmi yóò run àwọn ̀rẹ níwájú rẹ

èmi yóò lu àwọn ó kórìíra rẹ bolẹ̀.

24 Òtítọ́ mi àti ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ yóò pẹ̀rẹ

àti orúkọ mi ni a ó gbé ìwo rẹ ga.

25 Èmi ó gbé ọwọ́ rẹ lórí òkun,

àti ọwọ́ ̀tún rẹ lórí àwọn odo ńlá.

26 Òun yóò kígbe mi , Ìwọ ni baba mi, Ọlọ́run mi, àti àpáta ìgbàlà mi!

27 89.27: If 1.5. Èmi yóò ṣe é ni àkọ́mi,

ẹni gíga ju àwọn ọba ayé.

28 Títí láé ni èmi yóò pa ìfẹ́ dídúró ṣinṣin mọ́ fún un,

àti májẹ̀mi pẹ̀rẹ̀ yóò dúró gbọingbọin.

29 Èmi ó fi ìdí irú-ọmọ rẹ̀ múlẹ̀ títí láé,

àti ìtẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ ̀run ti láé.

30 "àwọn ọmọ rẹ̀ kọ òfin mi sílẹ̀

wọn rìn gẹ́gẹ́ ìlànà mi.

31 wọn ba ìlànà mi jẹ́

wọn pa àṣẹ mi mọ́,

32 nígbà náà ni èmi ó ̀gọ̀ bẹ ìrékọjá wọn ;

àti ̀ṣẹ̀ wọn pẹ̀pàṣán;

33 ṣùgbọ́n èmi ìfẹ́ mi ó dúró ṣinṣin kúrò lọ́dọ̀ rẹ,

bẹ́̀ ni èmi yóò jẹ́ òtítọ́ mi ó yẹ̀.

34 Èmi yóò sẹ́ májẹ̀mi,

bẹ́̀ ni èmi yóò ̀rọ̀ ó ti ẹnu mi jáde padà.

35 Lẹ́̀kan ṣoṣo ni èmi ti fi ìwà mímọ́ mi búra;

èmi yóò purọ́ fún Dafidi.

36 Irú-ọmọ rẹ yóò dúró títí láé,

àti ìtẹ́ rẹ̀ yóò dúró oòrùn níwájú mi.

37 89.37: If 1.5; 3.14. A ó fi múlẹ̀ títí láé òṣùpá,

àti bi ẹlẹ́rìí òtítọ́ ni ̀run." Sela.

38 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìwọ ti ṣá , ìwọ kórìíra;

ìwọ kún fún ìrunú ẹni àmì òróró rẹ.

39 Ìwọ ti sọ májẹ̀ìránṣẹ́ rẹ di òfo;

ìwọ tàbùkù adé rẹ nínú eruku.

40 Ìwọ ti gbogbo àwọn odi rẹ̀

ìwọ sọ ibi gíga rẹ̀ di ahoro.

41 Àwọn ń kọjá lọ fi ṣe ìjẹ;

ó ti di ̀gàn àwọn olùbágbé rẹ̀.

42 Ìwọ ti gbé ọwọ́ ̀tún ̀rẹ̀ sókè;

ìwọ gbogbo ̀rẹ̀ yọ̀.

43 Pẹ̀, ìwọ ti ojú idà rẹ̀ padà,

ìwọ dúró í nínú ogun.

44 Ìwọ ti ògo rẹ̀ kùnà,

ìwọ si ìtẹ́ rẹ̀ palẹ̀ sílẹ̀́lẹ̀.

45 Ìwọ ti ọjọ́ èwe rẹ̀ kúrú;

ìwọ fi ìtìjú ó.

46 Yóò ti pẹ́ , Olúwa?

ìwọ ó ha fi ara rẹ pamọ́ títí láé?

Yóò ti pẹ́ to ìbínú rẹ yóò máa iná?

47 Rántí ọjọ́ mi ti kúrú

nítorí asán ha ni ìwọ fi ṣẹ̀àwọn ènìyàn!

48 Ta ni yóò láààyè ikú rẹ̀?

Ta kúrò nínú agbára isà òkú?

49 Olúwa, níbo ni ìṣeun ìfẹ́ rẹ àtijọ́ ,

ìwọ ti fi òtítọ́ rẹ búra fún Dafidi?

50 Rántí, Olúwa, a ti ń gan àwọn ìránṣẹ́ rẹ;

èmi ti gbà àyà mi láti ̀dọ̀ àwọn ènìyàn,

51 ̀gàn àwọn ̀rẹ gàn, Olúwa,

wọn gan ipasẹ̀ ẹni àmì òróró rẹ.

52 Olùbùkún Olúwa títí láé.

Àmín àti Àmín.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-