Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 101

Ti Dafidi. Saamu.

1 Èmi yóò kọrin ìfẹ́ àti òdodo;

Olúwa, èmi yóò máa kọrin ìyìn.

2 Èmi yóò máa rin ìrìn mi pẹ̀ọgbọ́n láìlẹ́ṣẹ̀,

ìgbà wo ni ìwọ yóò ̀dọ̀ mi?

Èmi yóò máa rìn ilé mi

pẹ̀àyà pípé.

3 Èmi yóò gbé ohun búburú iwájú mi:

iṣẹ́ àwọn ó yapa ni èmi kórìíra.

Wọn yóò rọ̀ mọ́ mi.

4 Agídí ọkàn yóò kúrò lọ́dọ̀ mi;

èmi yóò mọ ènìyàn búburú.

5 Ẹnikẹ́ni ó ń sọ̀rọ̀ ẹnìkejì rẹ̀ ìkọ̀kọ̀,

òun èmi yóò kúrò

ẹni ó gbé ojú rẹ̀ ga ó ìgbéraga àyà,

òun èmi yóò faradà fún.

6 Ojú mi yóò lára àwọn olóòtítọ́ lórí ilẹ̀,

wọn ó máa mi gbé;

ẹni ó n rin ̀pípé

òun ni yóò máa sìn .

7 Ẹni ó ń ṣe ̀tàn, yóò gbé ilé mi,

ẹni ń ṣèké yóò dúró iwájú mi.

8 ojoojúmọ́ èmi yóò máa pa a lẹ́nu mọ

gbogbo àwọn ènìyàn búburú ilẹ̀ náà;

èmi yóò àwọn olùṣe búburú

kúrò ìlú Olúwa.

Veja também