Publicidade

Salmos 104

1 Yin Olúwa, ìwọ ọkàn mi.

Olúwa Ọlọ́run mi, ìwọ tóbi jọjọ;

ọlá àti ọláńlá ni ìwọ wọ̀ aṣọ.

2 Ìwọ fi ìmọ́lẹ̀ bo ara rẹ gẹ́gẹ́ aṣọ;

ó tẹ ̀run títẹ́ ẹní,

3 ìwọ ó fi omi ṣe ìtì igi àjà ìyẹ̀rẹ.

Ìwọ o ṣe àwọsánmọ̀ kẹ̀kẹ́ ogun rẹ

ìwọ ó ń rìn lórí apá ìyẹ́ afẹ́fẹ́.

4 Ó fi ̀fúùfù ṣe àwọn ìránṣẹ́ rẹ,

̀wọ́-iná ni àwọn olùránṣẹ́ rẹ.

5 O fi ayé gúnlẹ̀ lórí àwọn ìpìlẹ̀;

a le è láéláé.

6 Ìwọ fi ibú omi ó mọ́lẹ̀ aṣọ;

àwọn omi dúró lórí àwọn òkè ńlá.

7 Ṣùgbọ́n nípa ìbáwí rẹ ni àwọn omi lọ,

nípa ohùn àrá rẹ ni wọ́n sálọ.

8 wọ́n sàn kọjá lórí àwọn òkè,

wọ́n sọ̀kalẹ̀ lọ àwọn pẹ̀tẹ́lẹ̀,

ibi ìwọ ti yàn fún wọn.

9 Ìwọ gbé òpin wọn kọjá rẹ̀ kálẹ̀;

láéláé ni wọ́n bo ayé mọ́lẹ̀ lẹ́̀kan i.

10 Ìwọ ìsun da omi àwọn àfonífojì;

ó ń sàn láàrín àwọn òkè.

11 Wọ́n fún gbogbo àwọn ẹranko igbó omi

àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ń pa òǹgbẹ wọn.

12 Àwọn ẹyẹ ojú òfúrufú tẹ́ ìtẹ́ wọn lẹ́gbẹ̀́ omi

wọ́n ń kọrin láàrín àwọn ̀ka.

13 Ó bu omi rin àwọn òkè láti ìyẹ̀rẹ̀ ;

a tẹ́ ayé lọ́rùn nípa èso iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.

14 Ó koríko jáde fún àwọn ẹranko láti jẹ

àti àwọn ewébẹ̀ fún ènìyàn láti ,

ó oúnjẹ jáde láti ilẹ̀ .

15 Ọtí wáìnì ó ń ọkàn ènìyàn yọ̀,

òróró láti ojú rẹ̀ tan,

àti àkàrà láti ra ọkàn rẹ̀ padà.

16 Àwọn igi Olúwa ni a bu omi rin dáradára,

kedari ti Lebanoni ó gbìn.

17 Níbẹ̀ àwọn ẹyẹ ṣe ìtẹ́ wọn

ó ṣe àkọ̀ ni, orí igi gíga ni ilé rẹ̀.

18 Àwọn òkè gíga ni ààbò fún àwọn ewúrẹ́ igbó;

àti àwọn àlàpà jẹ́ ààbò fún àwọn ehoro.

19 Òṣùpá jẹ́ àmì fún àkókò

oòrùn mọ ìgbà yóò wọ̀.

20 Ìwọ òkùnkùn , ó di òru,

nínú èyí gbogbo ẹranko igbó ń rìn kiri.

21 Kìnnìún ń ramúramù fún ohun ọdẹ wọn

wọ́n ń oúnjẹ wọn láti ̀dọ̀ Ọlọ́run.

22 Oòrùn ràn, wọ́n ara wọn jọ,

wọn padà lọ dùbúlẹ̀ ihò wọn.

23 Ọkùnrin jáde lọ iṣẹ́ wọn,

àti làálàá rẹ̀ títí di àṣálẹ́.

24 Iṣẹ́ rẹ ti pọ̀ , Olúwa!

Nínú ọgbọ́n ni ìwọ ṣe gbogbo wọn:

ayé kún fún àwọn ìṣẹ̀á rẹ.

25 Bẹ́̀ ni Òkun yìí ó tóbi, ó ni ìbú,

ó kún fún àwọn ̀alààyè ìsàlẹ̀ láìníye

ohun alààyè tóbi àti kékeré.

26 Níbẹ̀ ni ọkọ̀ ń lọ síwá sẹ́yìn,

àti Lefitani, ìwọ láti ṣe àríyá nínú rẹ̀.

27 Àwọn wọ̀nyí ń ́

láti fún wọn oúnjẹ wọn lákòókò rẹ̀.

28 Nígbà ìwọ fi fún wọn,

wọn yóò jọ;

nígbà ìwọ la ọwọ́ rẹ̀,

a tẹ́ wọn lọ́rùn pẹ̀ohun rere.

29 Nígbà ìwọ pa ojú rẹ mọ́

ara rọ̀ wọ́n

nígbà ìwọ ̀wọn lọ,

wọn ó , wọn ó padà erùpẹ̀.

30 Nígbà ìwọ rán ̀rẹ,

ni a wọn,

ìwọ tún ojú ayé ṣe.

31 Jẹ́ ògo Olúwa pẹ́ títí láé;

inú Olúwa ó dùn ti iṣẹ́ rẹ̀,

32 ẹni ó wo ayé, ó wárìrì,

ẹni ó fọwọ́ tọ́ àwọn òkè, wọ́n yọ èéfín.

33 gbogbo ayé mi n ó kọrin Olúwa:

èmi ó kọrin ìyìn Olúwa

níwọ̀n ìgbà mo láààyè.

34 Jẹ́ ̀kọ́ mi ó tẹ́ lọ́rùn

mo ti ń yọ̀ nínú Olúwa.

35 Ṣùgbọ́n ẹlẹ́ṣẹ̀ kúrò láyé

ènìyàn búburú mọ́.

Yin Olúwa, ìwọ ọkàn mi.

Yin Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-