Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 12

Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ ti ṣeminiti. Saamu ti Dafidi.

1 Ràn lọ́wọ́, Olúwa, nítorí ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run mọ́;

olóòtítọ́ pòórá kúrò láàrín àwọn ènìyàn.

2 Olúkúlùkù ń parọ́ fún aládùúgbò rẹ̀;

ètè èké wọn ń sọ ̀tàn.

3 Olúwa ó ètè èké wọn

àti gbogbo ahọ́n ìfọ́nnu

4 ó ,

"Àwa ó borí pẹ̀ahọ́n wa;

àwa ètè wa, ta ni ̀wa?"

5 "Nítorí ìnilára àwọn aláìlágbára àti ìkérora àwọn aláìní,

Èmi yóò dìde nísinsin yìí," ni Olúwa .

"Èmi yóò dáàbò wọ́n lọ́wọ́ àwọn ń ṣe àrankàn wọn."

6 ̀rọ̀ Olúwa jẹ aláìlábùkù,

gẹ́gẹ́ fàdákà a yọ́ nínú ìléru amọ̀,

a sọ di mímọ́ nígbà méje.

7 Olúwa, ìwọ yóò pa mọ́

o gbà lọ́wọ́ àwọn ènìyàn wọ̀nyí títí láé.

8 Àwọn ènìyàn búburú ń rin ìrìn fáàrí kiri

nígbà wọn ń bọ̀wọ̀ fún òsì láàrín àwọn ènìyàn.

Veja também