Publicidade

Salmos 139

13 Nítorí ìwọ ni ó dá ọkàn mi;

ìwọ ni ó bò mí mọ́lẹ̀ nínú ìyá mi.

14 Èmi yóò yìn ọ, nítorí tẹ̀rù tẹ̀rù àti tìyanu tìyanu ní a dá mi;

ìyanu ní iṣẹ́ rẹ;

èyí nì ni ọkàn mi sì mọ̀ dájúdájú.

15 Ẹ̀dá ara mi kò pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ rẹ,

nígbà tí a dá mi ní ìkọ̀kọ̀.

Tí a sì ń ṣiṣẹ́ ní àràbarà ní ìhà ìsàlẹ̀ ilẹ̀ ayé,

16 ojú rẹ ti rí ohun ara mi

nígbà tí a kò tí ì ṣe mí pé,

àti nínú ìwé rẹ ni a ti kọ ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn sí,

ní ọjọ́ tí a dá wọn,

nígbà tí wọn kò tilẹ̀ tí ì sí.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-22_10-02-25-