Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 141

Saamu ti Dafidi.

1 Olúwa, èmi ́; yára ̀dọ̀ mi.

Gbọ́ ohùn mi, nígbà mo ń ́.

2 Jẹ́ àdúrà mi ó iwájú rẹ ẹbọ tùràrí

àti ìgbé ọwọ́ mi si òkè ẹbọ àṣálẹ́.

3 Fi ̀ṣọ́ ṣọ́ ẹnu mi, Olúwa:

o máa pa ìlẹ̀kùn ètè mi mọ́.

4 ṣe jẹ́ ọkàn mi ohun ń ṣe ibi,

láti máa àwọn ń ṣiṣẹ́ ̀ṣẹ̀ búburú

ṣe jẹ́ èmi jẹ àdídùn wọn.

5 Jẹ́ olódodo , ìṣeun ni ó jẹ́:

jẹ́ ó mi , ó jẹ́ òróró orí mi.

yóò fọ́ mi orí.

Síbẹ̀ àdúrà mi láìsí ìṣe àwọn olùṣe búburú.

6 A ó ju àwọn alákòóso sílẹ̀ láti bẹ̀bẹ̀ òkúta,

àwọn ẹni búburú yóò kọ àwọn ̀rọ̀ mi dùn.

7 Wọn yóò , "ẹni ó la aporo sórí ilẹ̀,

bẹ́̀ ni egungun wa tànkálẹ̀ ẹnu isà òkú."

8 Ṣùgbọ́n ojú mi ń bẹ lára rẹ, Olúwa Olódùmarè;

nínú rẹ̀ ni èmi ti ààbò, ṣe mi fún ikú.

9 Pa mọ́ kúrò nínú okùn wọn ti dẹ sílẹ̀ fún mi,

kúrò nínú ìkẹ́kùn àwọn oníṣẹ́ ̀ṣẹ̀.

10 Jẹ́ àwọn ẹni búburú ṣubú sínú àwọ̀n ara wọn,

nígbà èmi kọjá lọ láìléwu.

Veja também