Publicidade

Salmos 26

Ti Dafidi.

1 Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa,

nítorí mo ti ń rìn nínú ìwà òtítọ́ ̀ mi,

mo ti ìgbẹ́kẹ̀nínú Olúwa,

ǹjẹ́ ẹsẹ̀ mi yóò yẹ̀.

2 Wádìí mi , Ìwọ Olúwa, o dán mi ,

dán àyà àti ọkàn mi ;

3 nítorí ìfẹ́ ̀ rẹ ó dúró ṣinṣin ń bẹ níwájú mi,

èmí ti rìn nínú òtítọ́ rẹ.

4 Èmi jókòó pẹ̀aláìṣòótọ́,

bẹ́̀ ni èmi yóò àwọn àgàbàgebè wọlé.

5 Èmi ti kórìíra àwùjọ àwọn ènìyàn búburú

èmi yóò àwọn ènìyàn ìkà jókòó.

6 Èmí ó wẹ ọwọ́ mi àìlẹ́ṣẹ̀,

bẹ́̀ ni èmi yóò pẹpẹ rẹ Olúwa.

7 Èmi yóò kọrin sókè àní orin ọpẹ́,

èmi yóò máa sọ iṣẹ́ ìyanu rẹ̀.

8 Háà Olúwa, èmí ń fẹ́ ilé rẹ níbi ìwọ ń gbé,

àní níbi ògo rẹ̀ .

9 ṣe gbá mi dànù pẹ̀àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀,

tàbí ̀mi pẹ̀àwọn ọkùnrin òǹgbẹ ̀jẹ̀ ń gbẹ,

10 àwọn ọwọ́ wọn kún fún ìwà ibi,

ọwọ́ ̀tún wọn kún fún àbẹ̀tẹ́lẹ̀.

11 Ṣùgbọ́n èmi ó máa rìn nínú ìwà títọ́;

padà, o ṣàánú fún mi.

12 Ẹsẹ̀ mi dúró lórí ilẹ̀ ó tẹ́;

nínú ìjọ ńlá èmi yóò fi ìbùkún fún Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-