Publicidade

Salmos 31

Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi.

1 Nínú rẹ̀, Olúwa ni mo ti ààbò;

ṣe jẹ́ ojú ó ;

gbà nínú òdodo rẹ.

2 Tẹ́ etí rẹ mi,

gbà kíákíá;

jẹ́ àpáta ààbò mi,

jẹ́ odi alágbára láti gbà .

3 Ìwọ pàápàá ni àpáta àti ààbò mi,

nítorí orúkọ rẹ, máa ṣe olùtọ́ mi, o ṣe amọ̀mi.

4 Yọ jáde kúrò nínú àwọ̀n wọ́n dẹ pamọ́ fún mi,

nítorí ìwọ ni ìsádi mi.

5 ọwọ́ rẹ ni mo fi ̀mi ;

ìwọ ni o ti padà, Olúwa, Ọlọ́run òtítọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-