Publicidade

Salmos 41

Fún adarí orin. Saamu Dafidi.

1 Ìbùkún ni fún ẹni ó ń ro ti aláìní:

Olúwa yóò gbà á ìgbà ìpọ́njú.

2 Olúwa yóò dáàbò ó yóò pa ọkàn rẹ̀ mọ́:

yóò bùkún fún un orí ilẹ̀

fi sílẹ̀ fún ìfẹ́ àwọn ̀rẹ̀.

3 Olúwa yóò gbà á lórí àkéte àìsàn rẹ̀

yóò un padà bọ̀ sípò kúrò nínú àìsàn rẹ̀.

4 ti èmi, mo "Olúwa, ṣàánú fún mi;

sàn, nítorí mo ti ṣẹ̀ ".

5 Àwọn ̀mi ń sọ̀rọ̀ mi nínú àrankàn, ,

"Nígbà wo ni yóò , ti orúkọ rẹ̀ yóò run?"

6 Nígbàkígbà ẹnìkan ,

wọn ń sọ̀rọ̀ ̀tàn, nígbà àyà rẹ̀ ̀ṣẹ̀ jọ ara rẹ̀;

nígbà ó jáde lọ yóò máa tàn án kálẹ̀.

7 Àwọn ̀mi gbìmọ̀ papọ̀ nípa mi;

èmi ni wọ́n ń gbìmọ̀ ibi ,

8 wọ́n , "Ohun búburú ni ó mọ́ ọn ṣinṣin

àti ibi ó dùbúlẹ̀ ,

yóò dìde mọ́."

9 41.9: Jh 13.18. Pàápàá, ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́, ẹni mo gbẹ́kẹ̀,

ẹni ó ń jẹ nínú oúnjẹ mi,

gbé gìgísẹ̀ rẹ̀ sókè mi.

10 Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa, ṣàánú fún mi;

gbé mi sókè, ń ba san fún wọn.

11 Èmi mọ̀ inú rẹ̀ dùn mi,

nítorí ̀mi borí mi.

12 ó ṣe tèmi ni

ìwọ mímú nínú ìwà òtítọ́ mi

ìwọ gbé mi kalẹ̀ níwájú rẹ títí láé.

13 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,

láé àti láéláé.

Àmín àti Àmín.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-