Publicidade

Salmos 55

Fún adarí orin. Pẹ̀ohun èlò orin olókùn. Maskili ti Dafidi.

1 Fi etí àdúrà mi, Ọlọ́run,

ṣe fi ojú pa ̀bẹ̀ mi rẹ́:

2 gbọ́ mi o mi lóhùn.

Èrò mi ń láàmú, èmi ń pariwo.

3 ohùn àwọn ̀ni,

nítorí igbe àwọn ènìyàn búburú;

nítorí wọ́n ìjìyà sórí mi,

wọ́n kẹ́gàn mi nínú ìbínú wọn.

4 Ọkàn mi nínú ìrora pẹ̀;

̀ikú kọjú ìjà mi.

5 Ìbẹ̀àti ìwárìrì wa ara mi;

ìbẹ̀ti mọ́lẹ̀.

6 Èmi sọ , "Èmi ìbá ìyẹ́ àdàbà!

Èmi ìbá lọ n sinmi.

7 Èmi ìbá sálọ, jìnnà réré,

ń dúró aginjù;

8 èmi ìbá yára lọ́ si ibùgbé mi ibi ààbò,

jìnnà kúrò nínú ìjì àti ̀fúùfù líle."

9 Da àwọn ẹni búburú láàmú, Olúwa, da ahọ́n wọn ,

nítorí èmi ìwà agbára àti ìjà ìlú náà.

10 ̀sán àti òru ni wọ́n fi ń rìn gbogbo odi kiri;

ìwà ìkà àti èébú láàrín rẹ̀.

11 Ìwà búburú ń bẹ àárín rẹ̀;

̀tàn àti èké kúrò ìgboro rẹ̀.

12 ̀tàbùkù mi,

èmi yóò fi ara mọ́ ọn;

̀gbé ara rẹ̀ ga mi,

èmi ìbá pamọ́ fún un.

13 Ṣùgbọ́n ó ṣe ìwọ, ọkùnrin ẹgbẹ́ mi,

ẹlẹgbẹ́ mi, àti ̀rẹ́ ó súnmọ́ mi,

14 pẹ̀ẹni èmi ti jẹ ìgbádùn adùn ìdàpọ̀,

a ṣe ń rìn pẹ̀àwùjọ ilé Ọlọ́run.

15 ikú ó wọn,

wọn ó lọ láààyè isà òkú,

jẹ́ wọn ó sọ̀kalẹ̀ ibojì pẹ̀ìpayà,

nítorí ìwà búburú ń bẹ ibùjókòó wọn, àti nínú wọn.

16 Ṣùgbọ́n èmi pe Ọlọ́run;

Olúwa yóò gbà .

17 alẹ́, òwúrọ̀ àti ̀sán

èmi sọkún jáde nínú ìpọ́njú,

o gbọ́ ohùn mi.

18 Ó padà láìléwu

kúrò nínú ogun ó dìde mi,

nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó dìde mi.

19 Ọlọ́run yóò gbọ́, yóò pọ́n wọn lójú àní,

ẹni ó ti jókòó láti ìgbàanì Sela,

nítorí wọn àyípadà,

wọn bẹ̀Ọlọ́run.

20 ̀rẹ́ mi yìí ti dalẹ̀ èmi ̀rẹ́ rẹ̀;

ó ti ba májẹ̀rẹ̀ jẹ́.

21 ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ kúnná ju òrí-àmọ́,

ṣùgbọ́n ogun ni àyà rẹ̀;

̀rọ̀ rẹ̀ fẹ́lẹ́ ju òróró lọ,

ṣùgbọ́n idà fífàyọ wọn.

22 Gbé ẹrù rẹ lọ ̀dọ̀ Olúwa

yóò dúró;

òun jẹ́ olódodo ṣubú.

23 Ṣùgbọ́n ìwọ, Ọlọ́run, ni yóò mu àwọn ̀mi

ihò ìparun;

àwọn ẹni òǹgbẹ ̀jẹ̀ ń gbẹ àti ẹni ̀tàn,

yóò gbé ààbọ̀ ọjọ́ wọn.

Ṣùgbọ́n fún èmi, èmi gbẹ́kẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-