Publicidade

Salmos 57

Fún adarí orin. ohùn "ṣe parun." Ti Dafidi. Miktamu. Nígbà ó níwájú Saulu lọ sínú ihò òkúta.

1 Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run, ṣàánú fún mi,

nítorí nínú rẹ ni ààbò ọkàn .

Èmi o fi ààbò ibi ìyẹ́ apá rẹ

títí ewu yóò fi kọjá lọ.

2 Mo kígbe sókè Ọlọ́run ̀gá-ògo jùlọ,

Ọlọ́run ń pa májẹ̀rẹ̀ mọ́ fún mi.

3 Òun yóò ránṣẹ́ láti ̀run ,

yóò gbà , ẹni ń fẹ́ gbé mi

tilẹ̀ ń kẹ́gàn mi.

Ọlọ́run yóò rán àánú rẹ̀ àti òdodo rẹ̀ jáde.

4 Mo àárín àwọn kìnnìún;

mo dùbúlẹ̀ ni abẹ́ àwọn ̀búburú,

àwọn ènìyàn eyín wọn dàbí ̀kọ̀ àti ọfà

ẹni ahọ́n rẹ̀ jẹ́ idà mímú.

5 a yìn ́ Ọlọ́run, ju ̀run lọ,

ògo rẹ ju ti gbogbo ayé lọ.

6 Wọ́n ti ta àwọ̀n sílẹ̀ fún ẹsẹ̀ mi:

a tẹ orí ọkàn mi ba nínú ìtìjú,

wọ́n gbẹ́ kòtò ̀mi:

ṣùgbọ́n wọ́n ti síbẹ̀ fún ara wọn.

7 57.7-11: Sm 108.1-5. Ọkàn mi ti múra Ọlọ́run;

ọkàn mi ti múra, èmi ó kọrin, èmi ó si máa kọrin ìyìn.

8 , ìwọ ọkàn mi!

, ohun orin èlò àti dùùrù!

Èmi tìkára mi, yóò kùtùkùtù.

9 Èmi ó máa yìn ́, Olúwa, láàrín àwọn orílẹ̀-èdè;

èmi ó máa kọrin láàrín àwọn ènìyàn.

10 Nítorí títóbi ìfẹ́ rẹ, ó ̀run;

òtítọ́ rẹ tàn àwọsánmọ̀.

11 Gbígbéga ni ́, Ọlọ́run, ju àwọn ̀run lọ;

ògo rẹ ó ju gbogbo ayé lọ.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-