Publicidade

Salmos 62

Fún adarí orin. Fun Jedutuni. Saamu Dafidi.

1 Nínú Ọlọ́run nìkan ni ọkàn mi ti ìsinmi;

ìgbàlà mi ti ̀dọ̀ rẹ̀ .

2 Òun nìkan àpáta mi àti ìgbàlà mi;

Òun ni ààbò mi, a yóò mi ipò padà.

3 ̀yin ó ti máa kọ́ènìyàn kan pẹ́ ?

Gbogbo yín ni ó fẹ́ pa á,

ògiri ó fẹ́ yẹ̀, àti ọgbà ń lọ?

4 Kìkì èrò wọn ni láti ṣubú

kúrò nínú ọlá rẹ̀;

inú wọn dùn irọ́.

Wọ́n ń fi ẹnu wọn súre,

ṣùgbọ́n wọ́n ń gégùn ún nínú ọkàn wọn. Sela.

5 Nínú Ọlọ́run nìkan ni ìsinmi , ìwọ Ọlọ́run mi.

Ìrètí mi láti ̀dọ̀ rẹ.

6 Òun nìkan àpáta àti ìgbàlà mi;

Òun ni ààbò mi, a yóò ṣí mi ipò.

7 Ìgbàlà mi àti ògo mi dúró nínú Ọlọ́run;

Òun àpáta ńlá mi, àti ààbò mi.

8 Gbẹ́kẹ̀gbogbo ìgbà, ̀yin ènìyàn;

ọkàn rẹ jáde i,

nítorí Ọlọ́run ni ààbò wa.

9 Nítòótọ́, asán ni àwọn ọmọ ènìyàn,

èké ni àwọn olóyè,

wọ́n gòkè nínú ìwọ̀n,

lápapọ̀ wọ́n jẹ́ èémí.

10 ṣe gbẹ́kẹ̀ìnilára,

tàbí gbéraga nínú olè jíjà,

nítòótọ́ ọrọ̀ rẹ̀ ń pọ̀ i,

ṣe gbẹ́kẹ̀ rẹ wọn.

11 Ọlọ́run ti sọ̀rọ̀ lẹ́̀kejì,

ni mo gbọ́ èyí ,

"Ti Ọlọ́run ni agbára,

12 pẹ̀lúpẹ̀, Olúwa, tìrẹ ni àánú;

nítorí ìwọ san án fún olúkúlùkù ènìyàn gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-