Publicidade

Salmos 67

Fún adarí orin. Pẹ̀ohun èlò orin olókùn. Saamu. Orin.

1 Ọlọ́run ó ṣàánú fún wa ó bùkún fún wa,

ó jẹ́ ojú rẹ̀ tàn wa ,

2 ̀rẹ le di mọ̀ ayé,

ìgbàlà rẹ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè.

3 àwọn ènìyàn ó yìn ́, Ọlọ́run;

gbogbo ènìyàn ó yìn ́!

4 orílẹ̀-èdè ó yọ̀, ó kọrin fún ayọ̀,

nítorí ìwọ fi òdodo darí àwọn ènìyàn,

ìwọ jẹ ọba àwọn orílẹ̀-èdè ayé.

5 àwọn ènìyàn ó yìn ́, Ọlọ́run;

gbogbo ènìyàn ó yìn ́. Sela.

6 Nígbà náà ilẹ̀ yóò ìkórè rẹ̀ , Ọlọ́run,

Ọlọ́run wa, yóò bùkún fún wa.

7 Ọlọ́run yóò bùkún fún wa,

àti gbogbo òpin ilẹ̀ ayé yóò máa bẹ̀rẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-