Publicidade

Salmos 90

Àdúrà Mose ènìyàn Ọlọ́run.

1 Olúwa, ìwọ ti jẹ́ ibùgbé wa gbogbo ìran ìran.

2 a àwọn òkè ńlá

àti ìwọ ilẹ̀ àti ayé,

láti ayérayé ayérayé ìwọ ni Ọlọ́run.

3 Ìwọ ènìyàn padà erùpẹ̀,

, "Padà erùpẹ̀, ìwọ ọmọ ènìyàn."

4 90.4: 2Pt 3.8. Nítorí ìgbà ẹgbẹ̀rún (1,000) ọdún kọjá lójú rẹ,

àná ni ó , ìgbà ìṣọ́ kan lóru.

5 Ìwọ gbá ènìyàn dànù nínú oorun ikú;

wọ́n dàbí koríko tuntun òwúrọ̀.

6 Lóòtítọ́, òwúrọ̀, ó yọ tuntun

àṣálẹ́ ni yóò gbẹ, yóò rẹ̀ dànù.

7 A pa run nípa ìbínú rẹ

nípa ìbínú rẹ ara rọ̀ .

8 Ìwọ ti gbé ̀ṣẹ̀ wa ka iwájú rẹ,

àti ohun ìkọ̀kọ̀ wa nínú ìmọ́lẹ̀ iwájú rẹ.

9 Gbogbo ọjọ́ wa ń kọjá lọ lábẹ́ ìbínú rẹ;

àwa ń lo ọjọ́ wa lọ àlá à ń rọ́.

10 Àádọ́rin ọdún ni iye ọjọ́ ọdún ,

bi ó ṣe nípa agbára

wọn ọgọ́rin ọdún,

agbára nínú làálàá pẹ̀ìbànújẹ́ ni,

nítorí a pẹ́ e kúrò,

àwa a lọ.

11 Ta ni ó mọ agbára ìbínú rẹ?

Gẹ́gẹ́ ̀rẹ, bẹ́̀ ni ìbínú rẹ.

12 Kọ́ wa a ti ń kaye ọjọ́ wa dáradára,

àwa ba à fi ọkàn wa sípa ọgbọ́n.

13 Yípadà, Olúwa! Yóò ti pẹ́ ?

Ṣàánú fún àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ.

14 Tẹ́ wa lọ́rùn òwúrọ̀ nínú ìṣeun ìfẹ́ rẹ,

àwa ó kọrin fún ayọ̀

inú wa dùn gbogbo ọjọ́.

15 inú wa dùn ọjọ́ ìwọ ti pọ́n wa lójú,

fún ọjọ́ púpọ̀ àwa ti wàhálà.

16 Jẹ́ a fi iṣẹ́ rẹ̀ han àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀,

ògo rẹ̀ àwọn ọmọ wọn.

17 Jẹ́ ẹwà Olúwa Ọlọ́run wa lára wa;

fi ìdí iṣẹ́ ọwọ́ wa múlẹ̀ lára wa,

bẹ́̀ ni, ó fi ìdí iṣẹ́ ọwọ́ wa múlẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-