Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 96

1 96.1-13: 1Ki 16.23-33. kọrin tuntun Olúwa,

kọrin Olúwa gbogbo ayé.

2 kọrin Olúwa, yin orúkọ rẹ̀

sọ ti ìgbàlà rẹ̀ ọjọ́ ọjọ́.

3 sọ ti ògo rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè

àti iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ láàrín gbogbo ènìyàn.

4 Nítorí títóbi Olúwa ẹni ìyìn tọ́ ;

òun o yẹ a bẹ̀ju gbogbo òrìṣà lọ.

5 Nítorí asán ni gbogbo àwọn òrìṣà orílẹ̀-èdè

ṣùgbọ́n Olúwa àwọn ̀run.

6 Ọlá àti ọláńlá iwájú rẹ̀

agbára àti ògo ibi mímọ́ rẹ̀.

7 fi fún Olúwa, ̀yin ìbátan ènìyàn,

fi agbára àti ògo fún Olúwa.

8 fi ògo ó tọ́ Olúwa fún un;

ọrẹ , àgbàlá rẹ̀.

9 máa sin Olúwa nínú ẹwà ìwà mímọ́ rẹ̀;

wárìrì níwájú rẹ̀ gbogbo ayé.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também