Pular para o conteúdo
Publicidade

Salmos 10

1 Èéha ti ṣe, Olúwa, ìwọ fi dúró òkè réré?

Èéha ti ṣe, ìwọ fi ara rẹ pamọ́ ìgbà ìpọ́njú?

2 Nínú àrékérekè ni ènìyàn búburú mu aláìlera,

ẹni ti ó nínú ìdẹ̀kùn àrékérekè rẹ̀.

3 Nítorí ènìyàn búburú ń ṣògo ìfẹ́ inú ọkàn rẹ̀;

Ó bùkún olójúkòkòrò, ó ń kẹ́gàn Olúwa.

4 Ènìyàn búburú nínú ìgbéraga rẹ̀;

ààyè fún Ọlọ́run nínú gbogbo èrò rẹ̀.

5 ̀rẹ̀ ń gún régé nígbà gbogbo;

òun ń gbéraga, òfin rẹ̀ jìnnà i;

òun kẹ́gàn àwọn ̀rẹ̀.

6 O fún ara rẹ̀, "ohun ó .

Inú mi yóò máa dùn nígbà gbogbo, èmi wàhálà."

7 10.7: Ro 3.14. Ẹnu rẹ̀ kún fún ègún àti irọ́ àti ìtànjẹ;

wàhálà àti ohun búburú lábẹ́ ahọ́n rẹ̀.

8 Ó lúgọ bùba nítòsí ìletò.

Ò gọ níbi ìkọ̀kọ̀ láti pa aláìṣẹ̀.

Ojú rẹ̀ ń ṣọ́ àwọn tálákà ìkọ̀kọ̀.

9 Ó ba bùba i kìnnìún nínú pàǹtí;

Ó ba bùba láti àwọn aláìní ìrànwọ́;

ó àwọn aláìlólùrànlọ́wọ́, ó wọ́ wọn lọ sínú àwọ̀n rẹ̀.

10 Ó ba, ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀;

tálákà ba à le bọ́ ọwọ́ agbára rẹ̀.

11 Ó fún ara rẹ̀, "Ọlọ́run ti gbàgbé;

Ó pa ojú rẹ̀ mọ́, òun yóò i láéláé."

12 Dìde, Olúwa! Gbé ọwọ́ rẹ sókè, Ọlọ́run.

ṣe gbàgbé àwọn olùpọ́njú.

13 Èéṣe ènìyàn búburú ṣe ń kẹ́gàn Ọlọ́run?

Èéṣe o fi nínú ọkàn ara rẹ̀,

"láti ṣe ìṣirò"?

14 Ṣùgbọ́n ìwọ, Ọlọ́run, ni ó wàhálà àti ìrora;

Ìwọ láti fi ọwọ́ rẹ.

Tálákà fi ara rẹ̀ fún ;

Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ àwọn aláìní baba.

15 Ṣẹ́ apá àwọn ènìyàn búburú àti ènìyàn ibi;

é láti ṣírò fún ìwà ìkà rẹ̀

a le è .

16 Olúwa ń jẹ ọba láé àti láéláé;

àwọn orílẹ̀-èdè yóò ṣègbé lórí ilé rẹ.

17 Ìwọ́ gbọ́, Olúwa, ìfẹ́ àwọn a ni lára;

Ìwọ gbà wọ́n níyànjú, ó gbọ́ igbe wọn,

18 láti ṣe ìdájọ́ àwọn aláìní baba àti àwọn ti a ni lára,

ọkùnrin, ó ayé,

ó ṣe dẹ́rùbà ni mọ́.

Veja também