Pular para o conteúdo
Publicidade

Saamu 20

6 Nísinsin yìí, èmi mọ̀ ,

Olúwa pa ẹni àmì òróró rẹ̀ mọ́.

Yóò gbọ́ láti ̀run mímọ́ rẹ̀

pẹ̀agbára ìgbàlà ọwọ́ ̀tún rẹ̀.

7 Àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn kẹ̀kẹ́, àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn ẹṣin,

ṣùgbọ́n àwa gbẹ́kẹ̀orúkọ Olúwa Ọlọ́run wa.

8 Wọ́n wólẹ̀, eékún, wọ́n ṣubú,

ṣùgbọ́n àwa dìde, a dúró ṣinṣin.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também